An-Nas

الناس

Mankind6 ayahsMeccan

بِسْمِ ٱللَّهِ ٱلرَّحْمَٰنِ ٱلرَّحِيمِ

قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلنَّاسِ﴿١

1Sọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,

مَلِكِ ٱلنَّاسِ﴿٢

2Ọba àwọn ènìyàn,

إِلَٰهِ ٱلنَّاسِ﴿٣

3Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,[1]

مِن شَرِّ ٱلۡوَسۡوَاسِ ٱلۡخَنَّاسِ﴿٤

4níbi aburú (aṣ-Ṣaetọ̄n) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu[1]).

ٱلَّذِي يُوَسۡوِسُ فِي صُدُورِ ٱلنَّاسِ﴿٥

5(aṣ-Ṣaetọ̄n ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.

مِنَ ٱلۡجِنَّةِ وَٱلنَّاسِ﴿٦

6(Ṣaetọ̄n náà) wà nínú àwọn àlùjànnú àti àwọn ènìyàn.”

RELATED SURAHS